in

See the Yoruba national anthem Ambode wants students to sing

Students and pupils in Lagos State private and public schools will soon begin singing the National Anthem in Yoruba, according to Mr Akinwunmi Ambode.

The deputy governor, Mrs Idiat Adebule revealed the plan at a meeting with principals and school heads.
Here’s a version of the anthem and pledge in Yoruba:

VERSE 1

Dide eyin ara

Waka je ipe Naijiria

K’a fife sin ‘le wa

Pel’okun at’igbagbo

Kise awon akoni wa,

ko mase ja s’asan

K’a sin t’okan tara

Ile t’ominira,at’al

aafia

So d’okan

 

VERSE 2

Olorun Eleda

To ipa ona wa

F’ona han asaaju

K’odo wa m’otito

K’ododo at’ife po sii

K’aye won je pipe

So won d’eni giga

K’alafia oun eto le

Joba ni ‘le wa

 

THE PLEDGE

Mo se ileri fun Orile-Ede mi Naijiria,

Lati je olododo, eniti o see f’okan tan

Ati olotito eniyan

Lati sin in pelu gbogbo agbara mi,

Lati sa ipa mi gbogbo fun isokan re

Ati lati gbe e ga fun iyi ati ogo re.

Ki Olorun ran mi l’owo

Encomium

Written by Encomium

A media, tech and events company.

What do you think?

22 Points
Upvote Downvote

Leave a Reply

Avatar

Your email address will not be published. Required fields are marked *

Check Donald Trump’s true net worth

Ambode receives Nigerian World Record holder in Longest Reading Marathon